a
Mk 8.31
;
9.31
;
10.33
.
Mark 9:12
12
a
Ó sì dáhùn ó sì wí fún wọn pé,
“Lóòótọ́ ni Elijah yóò kọ́kọ́ dé yóò sì mú nǹkan gbogbo padà bọ̀ sípò. Àní gẹ́gẹ́ bí a ti kọ̀wé rẹ nípa ti Ọmọ Ènìyàn pé kò le ṣàìmá jìyà ohun púpọ̀ àti pé a ó sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Copyright information for
YorBMYO